Ìtàn isedale Yoruba

Table of Contents

Subject ; Yoruba

Class : Basic 6

Term : Third Term

Week :Week 10

Previous Knowledge : Learners have previous knowledge of how the Yoruba migrated from Meca to ILE Ifè

Behavioural Objectives b By the end of the lessons, learners will be able to

  • Say the founder of yorùbá land
  • Explain how the Yoruba migrated and form the new Yoruba land
  • Mention the children of Odùduwà

Content

  1. Lamurudu ni bàbá ńlá àwa Yoruba
  2. Ilu meeka ni Lamurudu wá láti ìbéèrè pẹpẹ, elesin iborisha nii
  3. Lamurudu bí ọmọkùnrin kan tí orúkọ rẹ njẹ Odùduwà (ODU TI O DA ÌWÀ)
  4. Odùduwà náà bí ọmọ ọkùnrin kan tí òrùlé rẹ NJẸ ỌKÀN BÍ (ÌDÈ Ó ṢE RÒ AKE)
  5. Okanbi fe Ọmọnide ni ìyá wo, wọn bí ọmọ méjì, láti ọmọ Okanbi là tí tán kalẹ
  6. Okanbi kú síwájú Odùduwà, Odùduwà ni ó tó àwọn ọmọ wonyi
  7. Nígbà tí tí wọn dàgbà, wọn pín ogún bàbà wọn, ká kúkú wọn sì lọ tèdó sí ikú kankan
  8. Lamurudu ni abore kan tí ó man nba bo àwọn òrìṣà rẹ, wọn má ń bá ṣe ọdún iborisha, orúkọ abore rẹ ni Asara
  9. Asara yìí bí ọmọ ọkùnrin kan tí orulo rẹ njẹ Buraimoh, inú ẹṣin ìbòrí sá ni wọn bíi sì
  10. Nigbati Buraimoh dàgbà, tí òye yee, ó kéde esin fún àwọn ará ìlú
  11. Ó ní kí wọn má tẹle ìsìn àwọn bàbà òun, ohun tí wọn bo ti kólé sors
  12. Lọ́jọ́ kan, leyin ti àwọn elesin aborisa yìí pariwo ọdún wọn, Buraimoh kò gbogbo ère òrìṣà wọn jo, ó sì dáná sún wọn
  13. Inú bíi àwọn elesin iborisa yìí, wọn si fii ìjà peeta, nínú rògbòdìyàn ìjà ẹṣin yìí ni Lamurudu kuu sì
  14. Wọn lé Odùduwà kúrò ní ìlú Mekka pelu awon eniyan rèé.
  15. Odidi adorun ojo ni Odùduwà fi rìn láti ìlú meeka kí ó tó dé ilé iife tí ó tèdó sii
  16. Ní ilé ìfẹ́, Odùduwà bá SETILU nibe, AGBONMIREGUN (ojogbon imo àti ọgbọ́n)
  17. Ní ilé ìfẹ́, wọn fi Odùduwà jọba Yoruba, èyí rìn ṣeé OONI àkọ́kọ́
  18. Ilé ìfẹ́ yìí ni àwa ọmọ Yoryba gba gbọ̀ gege bí orírun wà rírí di òní oloni
  19. Àwọn elesin musulumi tún lépa Odùduwà làti paa
  20. Pẹ̀lú àti leyin SETILU, Odùduwà segun wọn, wọn gba iwe ti wọn dii ni gbìn rìn sílè lowo wọn, a npe ni ÌDÍ